ẸKISODU 11
Mose Kéde Ikú Àwọn Àkọ́bí 1 Nígbà tí ó yá, OLUWA sọ fún Mose pé, “Ó ku ìyọnu kan péré, tí n óo mú bá Farao ati ilẹ̀ Ijipti, lẹ́yìn…
Mose Kéde Ikú Àwọn Àkọ́bí 1 Nígbà tí ó yá, OLUWA sọ fún Mose pé, “Ó ku ìyọnu kan péré, tí n óo mú bá Farao ati ilẹ̀ Ijipti, lẹ́yìn…
Àjọ Ìrékọjá 1 OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni ní ilẹ̀ Ijipti pé, 2 “Oṣù yìí ni yóo jẹ́ oṣù kinni ọdún fún yín. 3 Ẹ sọ fún gbogbo ìjọ…
Yíya Àwọn Àkọ́bí sí Mímọ́ 1 OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Ya gbogbo àwọn àkọ́bí sí mímọ́ fún mi, ohunkohun tí ó bá ti jẹ́ àkọ́bí láàrin àwọn eniyan…
Líla Òkun Pupa Kọjá 1 OLUWA bá rán Mose, ó ní, 2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọ́n yipada, kí wọ́n sì pàgọ́ siwaju Pi Hahirotu, láàrin Migidoli…
Orin Mose 1 Lẹ́yìn náà, Mose ati àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí sí OLUWA, wọ́n ní: “N óo kọrin sí OLUWA, nítorí pé, ó ti ja àjàṣẹ́gun tí ó…
Mana ati Àparò 1 Nígbà tí ó yá, gbogbo ìjọ eniyan Israẹli jáde kúrò ní Elimu, wọ́n lọ sí aṣálẹ̀ Sini tí ó wà ní ààrin Elimu ati Sinai, ní…
Omi Jáde láti Inú Àpáta 1 Gbogbo ìjọ eniyan Israẹli gbéra láti aṣálẹ̀ Sini, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí lọ láti ibùsọ̀ kan dé ekeji, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí OLUWA pa fún…
Jẹtiro Lọ Bẹ Mose Wò 1 Jẹtiro, alufaa àwọn ará Midiani, baba iyawo Mose, gbọ́ gbogbo ohun tí Ọlọrun ti ṣe fún Mose ati fún Israẹli, àwọn eniyan rẹ̀, ati…
Àwọn Ọmọ Israẹli ní Òkè Sinai 1 Ní oṣù kẹta tí àwọn eniyan Israẹli kúrò ní ilẹ̀ Ijipti ni wọ́n dé aṣálẹ̀ Sinai. 2 Refidimu ni wọ́n ti gbéra wá…
Òfin Mẹ́wàá 1 Ọlọrun sì sọ ọ̀rọ̀ wọnyii, ó ní, 2 “Èmi ni OLUWA Ọlọrun yín, tí ó mu yín jáde láti ilẹ̀ Ijipti, ní oko ẹrú tí ẹ wà:…