JEREMAYA 21
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Ìṣubú Jerusalẹmu 1 Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya gbọ́ lẹ́nu OLUWA nìyí nígbà tí ọba Sedekaya rán Paṣuri, ọmọ Malikaya, ati alufaa Sefanaya, ọmọ Maaseaya, sí i; 2 tí ọba…
Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Ìṣubú Jerusalẹmu 1 Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya gbọ́ lẹ́nu OLUWA nìyí nígbà tí ọba Sedekaya rán Paṣuri, ọmọ Malikaya, ati alufaa Sefanaya, ọmọ Maaseaya, sí i; 2 tí ọba…
Iṣẹ́ tí Jeremaya Jẹ́ fún Ìdílé Ọba Juda 1 OLUWA sọ fún mi pé, kí n lọ sí ilé ọba Juda kí n sọ fún un níbẹ̀ pé, 2 “Gbọ́…
Ìrètí Ọjọ́ Iwájú 1 OLUWA ní, “Àwọn olùṣọ́-aguntan tí wọn ń tú àwọn agbo aguntan mi ká, tí wọn ń run wọ́n gbé!” 2 Nítorí náà, OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ…
Apẹ̀rẹ̀ Èso Ọ̀pọ̀tọ́ Meji 1 Lẹ́yìn tí Nebukadinesari, ọba Babiloni ti kó Jehoiakini ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu kúrò ní ìlú Jerusalẹmu lọ sí Babiloni, pẹlu àwọn ìjòyè Juda, ati àwọn…
Àwọn Ọ̀tá láti Ìhà Àríwá 1 Ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu, ọmọ Josaya jọba ní Juda, tí ó jẹ́ ọdún kinni tí Nebukadinesari jọba Babiloni, Jeremaya wolii gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA…
A Pe Jeremaya Lẹ́jọ́ 1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Jehoiakimu ọba Juda, ọmọ Josaya, 2 OLUWA bá mi sọ̀rọ̀; ó ní, “Dúró sí gbọ̀ngàn ilé OLUWA, kí o sọ gbogbo ọ̀rọ̀…
Jeremaya Kọrùn Bọ Àjàgà 1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ọmọ Josaya, OLUWA bá èmi Jeremaya sọ̀rọ̀; ó ní: 2 “Ṣe àjàgà kan pẹlu okùn rẹ̀ kí o sì…
Wolii Jeremaya ati Wolii Hananaya 1 Ní ọdún kan náà, ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ní oṣù karun-un ọdún kẹrin, Hananaya wolii ọmọ Aṣuri, tí ó wá láti Gibeoni…
Lẹta Jeremaya sí Àwọn Tí Ogun Kó Lọ sí Babiloni 1 Jeremaya wolii kọ ìwé kan ranṣẹ láti Jerusalẹmu, ó kọ ọ́ sí àwọn àgbààgbà láàrin àwọn tí a kó…
Ìlérí OLUWA fún Àwọn Eniyan Rẹ̀ 1 OLUWA Ọlọrun Israẹli bá Jeremaya sọ̀rọ̀: 2 Ó ní, “Kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún ọ sinu ìwé, 3 nítorí pé…