JEREMAYA 21

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Ìṣubú Jerusalẹmu 1 Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya gbọ́ lẹ́nu OLUWA nìyí nígbà tí ọba Sedekaya rán Paṣuri, ọmọ Malikaya, ati alufaa Sefanaya, ọmọ Maaseaya, sí i; 2 tí ọba…

JEREMAYA 22

Iṣẹ́ tí Jeremaya Jẹ́ fún Ìdílé Ọba Juda 1 OLUWA sọ fún mi pé, kí n lọ sí ilé ọba Juda kí n sọ fún un níbẹ̀ pé, 2 “Gbọ́…

JEREMAYA 23

Ìrètí Ọjọ́ Iwájú 1 OLUWA ní, “Àwọn olùṣọ́-aguntan tí wọn ń tú àwọn agbo aguntan mi ká, tí wọn ń run wọ́n gbé!” 2 Nítorí náà, OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ…

JEREMAYA 24

Apẹ̀rẹ̀ Èso Ọ̀pọ̀tọ́ Meji 1 Lẹ́yìn tí Nebukadinesari, ọba Babiloni ti kó Jehoiakini ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu kúrò ní ìlú Jerusalẹmu lọ sí Babiloni, pẹlu àwọn ìjòyè Juda, ati àwọn…

JEREMAYA 25

Àwọn Ọ̀tá láti Ìhà Àríwá 1 Ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu, ọmọ Josaya jọba ní Juda, tí ó jẹ́ ọdún kinni tí Nebukadinesari jọba Babiloni, Jeremaya wolii gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA…

JEREMAYA 26

A Pe Jeremaya Lẹ́jọ́ 1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Jehoiakimu ọba Juda, ọmọ Josaya, 2 OLUWA bá mi sọ̀rọ̀; ó ní, “Dúró sí gbọ̀ngàn ilé OLUWA, kí o sọ gbogbo ọ̀rọ̀…

JEREMAYA 27

Jeremaya Kọrùn Bọ Àjàgà 1 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ọmọ Josaya, OLUWA bá èmi Jeremaya sọ̀rọ̀; ó ní: 2 “Ṣe àjàgà kan pẹlu okùn rẹ̀ kí o sì…

JEREMAYA 28

Wolii Jeremaya ati Wolii Hananaya 1 Ní ọdún kan náà, ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekaya, ọba Juda, ní oṣù karun-un ọdún kẹrin, Hananaya wolii ọmọ Aṣuri, tí ó wá láti Gibeoni…

JEREMAYA 29

Lẹta Jeremaya sí Àwọn Tí Ogun Kó Lọ sí Babiloni 1 Jeremaya wolii kọ ìwé kan ranṣẹ láti Jerusalẹmu, ó kọ ọ́ sí àwọn àgbààgbà láàrin àwọn tí a kó…

JEREMAYA 30

Ìlérí OLUWA fún Àwọn Eniyan Rẹ̀ 1 OLUWA Ọlọrun Israẹli bá Jeremaya sọ̀rọ̀: 2 Ó ní, “Kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún ọ sinu ìwé, 3 nítorí pé…