KỌRINTI KINNI 1

Ìkíni 1 Èmi Paulu, tí Ọlọrun pè láti jẹ́ òjíṣẹ́ Kristi Jesu, ati Sositene arakunrin wa ni à ń kọ ìwé yìí– 2 Sí ìjọ Ọlọrun ti ó wà ní…

KỌRINTI KINNI 2

Paulu Ń Waasu Kristi Tí Wọ́n Kàn Mọ́ Agbelebu 1 Ẹ̀yin ará, nígbà tí mo dé ọ̀dọ̀ yín, n kò wá fi ọ̀rọ̀ dídùn tabi ọgbọ́n eniyan kéde àṣírí Ọlọrun…

KỌRINTI KINNI 3

Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ pẹlu Ọlọrun 1 Ẹ̀yin ará, n kò lè ba yín sọ̀rọ̀ bí ẹni ti Ẹ̀mí, bíkòṣe bí ẹlẹ́ran-ara, àní gẹ́gẹ́ bí ọmọ-ọwọ́ ninu Kristi. 2 Wàrà ni mo ti…

KỌRINTI KINNI 4

Iṣẹ́ Àwọn Aposteli 1 Bí ó ti yẹ kí eniyan máa rò nípa wa ni pé a jẹ́ iranṣẹ Kristi ati ìríjú àwọn nǹkan àṣírí Ọlọrun. 2 Ohun tí à…

KỌRINTI KINNI 5

Paulu Ṣe Ìdájọ́ lórí Ìwà Ìbàjẹ́ 1 A gbọ́ dájúdájú pé ìwà àgbèrè wà láàrin yín, irú èyí tí kò tilẹ̀ sí láàrin àwọn tí kì í ṣe Juu. A…

KỌRINTI KINNI 6

Onigbagbọ Ń Pe Ara Wọn Lẹ́jọ́ Níwájú Àwọn Alaigbagbọ 1 Kí ló dé tí ẹni tí ó bá ní ẹ̀sùn sí ẹnìkejì rẹ̀ fi ń gbé ẹjọ́ lọ siwaju àwọn…

KỌRINTI KINNI 7

Èrò nípa Igbeyawo 1 Ọ̀rọ̀ lórí àwọn nǹkan tí ẹ kọ nípa rẹ̀, ó dára tí ọkunrin bá lè ṣe é kí ó má ní obinrin rara. 2 Ṣugbọn nítorí…

KỌRINTI KINNI 8

Oúnjẹ Tí A Fi Rúbọ fún Oriṣa 1 Ó wá kan ọ̀rọ̀ nípa àwọn nǹkan tí a fi rúbọ fún oriṣa. A mọ̀ pé, “Gbogbo wa ni a ní ìmọ̀,”…

KỌRINTI KINNI 9

Iṣẹ́ ati Ẹ̀tọ́ Aposteli 1 Ṣebí mo ní òmìnira? Ṣebí aposteli ni mí? Ṣebí mo ti rí Jesu Oluwa wa sójú? Ṣebí àyọrísí iṣẹ́ mi ninu Oluwa ni yín? 2…

KỌRINTI KINNI 10

Ìkìlọ̀ Nípa Ìbọ̀rìṣà 1 Ẹ̀yin ará, ẹ má gbàgbé pé gbogbo àwọn baba wa ni wọ́n wà lábẹ́ ìkùukùu. Gbogbo wọn ni wọ́n la òkun kọjá. 2 Gbogbo wọn ni…