KRONIKA KINNI 21
Dafidi Ṣe Ètò Ìkànìyàn 1 Satani fẹ́ ta jamba fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí náà ó gbó Dafidi láyà láti kà wọ́n. 2 Dafidi sọ fún Joabu ati àwọn ọ̀gágun…
Dafidi Ṣe Ètò Ìkànìyàn 1 Satani fẹ́ ta jamba fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí náà ó gbó Dafidi láyà láti kà wọ́n. 2 Dafidi sọ fún Joabu ati àwọn ọ̀gágun…
1 Nítorí náà Dafidi pàṣẹ pé, “Ibí yìí ni ilé OLUWA Ọlọrun, ati pẹpẹ ẹbọ sísun yóo wà fún Israẹli.” Ìpalẹ̀mọ́ fún Kíkọ́ Tẹmpili 2 Dafidi pàṣẹ pé kí gbogbo…
1 Nígbà tí Dafidi dàgbà, tí ó di arúgbó, ó fi Solomoni, ọmọ rẹ̀ jọba lórí Israẹli. Iṣẹ́ Àwọn Ọmọ Lefi 2 Dafidi pe gbogbo àwọn àgbààgbà Israẹli, àwọn alufaa…
Iṣẹ́ Àwọn Alufaa 1 Bí a ṣe pín àwọn ọmọ Aaroni nìyí: Aaroni ní ọmọkunrin mẹrin: Nadabu, Abihu, Eleasari ati Itamari. 2 Nadabu ati Abihu kú ṣáájú baba wọn láì…
Àwọn Akọrin Inú Tẹmpili 1 Dafidi ati àwọn olórí ogun ya àwọn kan sọ́tọ̀ ninu àwọn ọmọ Asafu, Hemani ati ti Jedutuni láti máa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nígbà tí wọ́n bá…
Àwọn Aṣọ́nà Tẹmpili 1 Bí a ti ṣe pín iṣẹ́ fún àwọn aṣọ́nà nìwọ̀nyí: Meṣelemaya, ọmọ Kore, ní ìdílé Asafu, ninu ìran Kora. 2 Meṣelemaya bí ọmọ meje, orúkọ wọn…
Àwọn Ológun ati Ètò Òṣèlú 1 Àwọn wọnyi ni àwọn olórí ìdílé ati olórí ẹgbẹẹgbẹrun ọmọ ogun ati olórí ọgọọgọrun-un ọmọ ogun, ati àwọn olórí tí wọ́n jẹ́ aṣojú ọba…
Ìlànà tí Dafidi Fi Lélẹ̀ fún Kíkọ́ Tẹmpili 1 Dafidi ọba pe gbogbo àwọn olórí ní ilẹ̀ Israẹli jọ sí Jerusalẹmu, àwọn olórí láàrin àwọn ẹ̀yà Israẹli, àwọn olórí àwọn…
Àwọn Ẹ̀bùn láti fi Kọ́ Tẹmpili 1 Dafidi ọba sọ fún àpéjọpọ̀ àwọn eniyan pé, “Solomoni ọmọ mi, ẹnìkan ṣoṣo tí Ọlọrun yàn, ó kéré, kò tíì ní ìrírí, iṣẹ́…