NEHEMAYA 1
1 Ìtàn Nehemaya ọmọ Hakalaya. Ẹ̀dùn Ọkàn Nehemaya fún Jerusalẹmu Ní oṣù Kisilefi, ní ogún ọdún tí Atasasesi jọba ní ilẹ̀ Pasia, mo wà ní Susa tíí ṣe olú-ìlú ilẹ̀…
1 Ìtàn Nehemaya ọmọ Hakalaya. Ẹ̀dùn Ọkàn Nehemaya fún Jerusalẹmu Ní oṣù Kisilefi, ní ogún ọdún tí Atasasesi jọba ní ilẹ̀ Pasia, mo wà ní Susa tíí ṣe olú-ìlú ilẹ̀…
Nehemaya lọ sí Jerusalẹmu 1 Ní oṣù Nisani, ní ogún ọdún tí Atasasesi ọba gorí oyè, mo gbé ọtí waini tí ó wà níwájú rẹ̀ fún un. N kò fajúro…
Títún Ògiri Jerusalẹmu Mọ 1 Eliaṣibu, Olórí alufaa, ati àwọn arakunrin rẹ̀ tí àwọn náà jẹ́ alufaa bíi rẹ̀ múra, wọ́n sì kọ́ Ẹnubodè Aguntan. Wọ́n yà á sí mímọ́…
Nehemaya Borí Ìṣòro Tí ó Dojú Kọ Iṣẹ́ Rẹ̀ 1 Nígbà tí Sanbalati gbọ́ pé a ti ń kọ́ odi náà, inú bíi gidigidi, ó bá bẹ̀rẹ̀ sí bu ẹnu…
Níni Àwọn Talaka Lára 1 Ọpọlọpọ àwọn eniyan náà, atọkunrin atobinrin, bẹ̀rẹ̀ sí tako àwọn Juu, arakunrin wọn. 2 Àwọn kan ń sọ pé, “Àwa, ati àwọn ọmọ wa, lọkunrin…
Wọ́n Dìtẹ̀ Mọ́ Nehemaya 1 Nígbà tí wọ́n sọ fún Sanbalati ati Tobaya ati Geṣemu ará Arabia ati àwọn ọ̀tá wa yòókù pé a ti tún odi náà mọ, ati…
1 Lẹ́yìn tí a ti mọ odi náà tán, tí mo ti ṣe àwọn ìlẹ̀kùn rẹ̀, tí mo sì ti yan àwọn olùṣọ́ ẹnu ọ̀nà, ati àwọn akọrin ati àwọn…
Ẹsira Ka Òfin fún Àwọn Eniyan náà 1 Ní ọjọ́ kinni oṣù náà, gbogbo wọn pátá péjọ pọ̀ sí gbangba ìta níwájú Ẹnubodè Omi, wọ́n sì sọ fún Ẹsira, akọ̀wé,…
Àwọn Eniyan náà Jẹ́wọ́ Ẹ̀ṣẹ̀ Wọn 1 Ní ọjọ́ kẹrinlelogun oṣù kan náà, àwọn ọmọ Israẹli péjọ pọ̀, wọ́n gbààwẹ̀, wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀, wọ́n sì ku eruku sí orí…
1 Àwọn tí wọ́n fi ọwọ́ sí ìwé náà tí wọ́n sì fi èdìdì dì í nìwọ̀nyí: Nehemaya, gomina, ọmọ Hakalaya, ati Sedekaya. 2 Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ alufaa wọnyi:…