NỌMBA 1
Ètò Ìkànìyàn Àkọ́kọ́ láàrin Àwọn Ọmọ Israẹli 1 Ní ọjọ́ kinni oṣù keji, ní ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, OLUWA sọ fún Mose ninu…
Ètò Ìkànìyàn Àkọ́kọ́ láàrin Àwọn Ọmọ Israẹli 1 Ní ọjọ́ kinni oṣù keji, ní ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ijipti, OLUWA sọ fún Mose ninu…
Ètò Pípa Àgọ́ Ní Ẹlẹ́yà-mẹ̀yà 1 OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé: 2 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli yóo bá pàgọ́ wọn, kí olukuluku máa pàgọ́ rẹ̀ lábẹ́ àsíá…
Àwọn Ọmọ Aaroni 1 Àwọn wọnyi ni ìdílé Aaroni ati ti Mose, nígbà tí OLUWA bá Mose sọ̀rọ̀ ní orí òkè Sinai. 2 Orúkọ àwọn ọmọ Aaroni lọkunrin nìwọ̀nyí: Nadabu…
Iṣẹ́ Àwọn Ọmọ Lefi–Ìdílé Kohati 1 OLUWA sọ fún Mose ati Aaroni pé: 2 “Ẹ ka iye àwọn ọmọ Kohati láàrin àwọn ọmọ Lefi, ní ìdílé-ìdílé, gẹ́gẹ́ bí ilé baba…
Àwọn Aláìmọ́ 1 OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọ́n lé gbogbo àwọn adẹ́tẹ̀ kúrò ní ibùdó wọn, gbogbo àwọn tí ó ni ọyún…
Òfin fún Àwọn Nasiri 1 OLUWA sọ fún Mose kí ó sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, 2 “Nígbà tí ọkunrin tabi obinrin kan bá ṣe ìlérí láti di Nasiri,…
Ẹbọ Àwọn Olórí 1 Ní ọjọ́ tí Mose gbé Àgọ́ Àjọ dúró, tí ó sì ta òróró sí i tòun ti gbogbo nǹkan tí ó wà ninu rẹ̀, ati pẹpẹ…
Ìgbékalẹ̀ Fìtílà 1 OLUWA rán Mose pé 2 kí ó sọ fún Aaroni pé, nígbà tí Aaroni bá tan fìtílà mejeeje, kí ó gbé wọn sórí ọ̀pá fìtílà kí wọ́n…
Àjọ Ìrékọjá Keji 1 Ní oṣù kinni, ọdún keji tí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní Ijipti, OLUWA sọ fún Mose ninu aṣálẹ̀ Sinai pé, 2 “Kí àwọn ọmọ Israẹli…
Àwọn Fèrè Fadaka 1 OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Fi fadaka tí wọ́n fi òòlù lù ṣe fèrè meji fún pípe àwọn ọmọ Israẹli jọ ati títú ibùdó palẹ̀….