NỌMBA 21

Ìṣẹ́gun lórí Àwọn Ará Kenaani 1 Nígbà tí ọba Aradi ará Kenaani tí ń gbé ìhà gúsù ní Nẹgẹbu Kenaani gbọ́ pé àwọn ọmọ Israẹli ń gba ọ̀nà Atarimu bọ̀,…

NỌMBA 22

Ọba Moabu Ranṣẹ Pe Balaamu 1 Àwọn ọmọ Israẹli ṣí kúrò, wọ́n lọ pa àgọ́ wọn sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní òdìkejì Jọdani tí ó kọjú sí Jẹriko. 2 Nígbà tí…

NỌMBA 23

Àsọtẹ́lẹ̀ Àkọ́kọ́ tí Balaamu Sọ 1 Balaamu sọ fún Balaki pé, “Tẹ́ pẹpẹ meje sí ibí yìí fún mi kí o sì pèsè akọ mààlúù meje ati àgbò meje.” 2…

NỌMBA 24

1 Nígbà tí Balaamu rí i pé OLUWA ń súre fún àwọn ọmọ Israẹli, kò lọ bíi ti iṣaaju láti bá OLUWA pàdé. Ṣugbọn ó kọjú sí aṣálẹ̀, 2 ó…

NỌMBA 25

Àwọn Ọmọ Israẹli ní Peori 1 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ sí àfonífojì Ṣitimu, àwọn ọkunrin wọn ń bá àwọn ọmọbinrin Moabu tí wọ́n wà níbẹ̀ ṣe àgbèrè. 2…

NỌMBA 26

Ètò Ìkànìyàn Keji 1 Lẹ́yìn àjàkálẹ̀ àrùn náà, OLUWA sọ fún Mose ati Eleasari alufaa ọmọ Aaroni pé, 2 “Ẹ ka iye àwọn ọmọ Israẹli, àwọn tí wọ́n tó ẹni…

NỌMBA 27

Àwọn Ọmọbinrin Selofehadi 1 Nígbà náà ni Mahila, Noa, Hogila, Milika ati Tirisa, àwọn ọmọbinrin Selofehadi, ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase, ti ìdílé Manase, ọmọ Josẹfu, 2…

NỌMBA 28

Ẹbọ Àtìgbàdégbà 1 OLUWA sọ fún Mose 2 pé kí ó pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọn máa mú ọrẹ wá fún ohun ìrúbọ sí òun OLUWA ní àkókò…

NỌMBA 29

Ẹbọ Àjọ̀dún Ọdún Titun 1 “Ní ọjọ́ kinni oṣù keje, ẹ óo máa ní àpèjọ mímọ́, ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ líle kankan. Ó jẹ́ ọjọ́ tí ẹ óo…

NỌMBA 30

Ìlànà nípa Ẹ̀jẹ́ Jíjẹ́ 1 Mose sọ fún àwọn olórí àwọn ẹ̀yà Israẹli àwọn ohun tí OLUWA pa láṣẹ: 2 Bí ọmọkunrin kan bá bá OLUWA jẹ́jẹ̀ẹ́ tabi tí ó…