NỌMBA 31

Wọ́n Dojú Ogun Mímọ́ kọ Midiani 1 OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Fìyà jẹ àwọn ará Midiani fún ohun tí wọ́n ṣe sí àwọn ọmọ Israẹli. Lẹ́yìn náà, o…

NỌMBA 32

Àwọn Ẹ̀yà Ìlà Oòrùn Jọdani 1 Nígbà tí àwọn ọmọ Reubẹni ati àwọn ọmọ Gadi, tí wọ́n ní ẹran ọ̀sìn pupọ, rí ilẹ̀ Jaseri ati ilẹ̀ Gileadi pé ibẹ̀ dára…

NỌMBA 33

Ìrìn Àjò láti Ijipti sí Moabu 1 Ibi tí àwọn ọmọ Israẹli pàgọ́ sí ninu ìrìn àjò wọn láti ìgbà tí wọn ti kúrò ní Ijipti lábẹ́ àṣẹ Mose ati…

NỌMBA 34

Àwọn Ààlà Ilẹ̀ náà 1 OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ Kenaani tí mo fun yín, gbogbo ilẹ̀…

NỌMBA 35

Àwọn Ìlú tí A Fún Àwọn Ọmọ Lefi 1 Ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní ìhà ìlà oòrùn Jọdani ní òdìkejì Jẹriko, OLUWA sọ fún Mose pé, 2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ…

NỌMBA 36

Ogún Àwọn Obinrin Abilékọ 1 Àwọn olórí ìdílé àwọn ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri ati ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu, wá sọ́dọ̀ Mose ati àwọn olórí ẹ̀yà Israẹli, 2 wọ́n ní, “OLUWA…