SAMUẸLI KINNI 11

Saulu Ṣẹgun Àwọn Ará Amoni 1 Nahaṣi, ọba Amoni, kó àwọn ọmọ ogun rẹ̀, wọ́n lọ gbógun ti ìlú Jabeṣi Gileadi. Àwọn ará Jabeṣi bá sọ fún Nahaṣi pé, “Jẹ́…

SAMUẸLI KINNI 12

Ọ̀rọ̀ ìdágbére Samuẹli 1 Lẹ́yìn náà, Samuẹli wí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Mo ti ṣe ohun tí ẹ ní kí n ṣe. Mo ti fi ẹnìkan jọba lórí yín….

SAMUẸLI KINNI 13

Àwọn Ọmọ Israẹli Gbógun ti Àwọn Ará Filistia 1 Saulu jẹ́ bíi ọmọ ọgbọ̀n ọdún… nígbà tí ó jọba lórí Israẹli. Ó sì wà lórí oyè fún bíi ogoji ọdún….

SAMUẸLI KINNI 14

Jonatani Hùwà Akikanju 1 Ní ọjọ́ kan, Jonatani, ọmọ Saulu, wí fún ọdọmọkunrin tí ó ń ru ihamọra rẹ̀ pé, “Jẹ́ kí á lọ sí òdìkejì ibùdó àwọn ọmọ ogun…

SAMUẸLI KINNI 15

Àwọn Ọmọ Israẹli Bá Àwọn Ará Amaleki Jagun 1 Samuẹli sọ fún Saulu pé, “OLUWA rán mi láti fi òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli, eniyan rẹ̀. Nisinsinyii gbọ́…

SAMUẸLI KINNI 16

Wọ́n Fi Àmì Òróró Yan Dafidi lọ́ba 1 OLUWA wí fún Samuẹli pé, “Ìgbà wo ni o fẹ́ káàánú lórí Saulu dà? Ṣebí o mọ̀ pé mo ti kọ̀ ọ́…

SAMUẸLI KINNI 17

Goliati Pe Àwọn Ọmọ Israẹli Níjà 1 Àwọn ọmọ ogun Filistini kó ara wọn jọ sí Soko, ìlú kan ní ilẹ̀ Juda láti bá Israẹli jagun. Wọ́n pa ibùdó wọn…

SAMUẸLI KINNI 18

1 Lẹ́yìn tí Dafidi ati Saulu parí ọ̀rọ̀ wọn, ọkàn Jonatani, ọmọ Saulu fà mọ́ Dafidi lọpọlọpọ ó sì fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀mí ara rẹ̀. 2 Saulu gba Dafidi…

SAMUẸLI KINNI 19

Saulu Fẹ́ Pa Dafidi 1 Saulu sọ fún ọmọ rẹ̀ Jonatani ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé kí wọ́n pa Dafidi. Ṣugbọn Jonatani fẹ́ràn Dafidi lọpọlọpọ. 2 Ó sì sọ…

SAMUẸLI KINNI 20

Jonatani Ran Dafidi lọ́wọ́ 1 Dafidi sá kúrò ní Naioti, ní Rama, lọ sọ́dọ̀ Jonatani, ó sì bi í pé, “Kí ni mo ṣe? Ìwà burúkú wo ni mo hù?…