KỌRINTI KINNI 9

Iṣẹ́ ati Ẹ̀tọ́ Aposteli 1 Ṣebí mo ní òmìnira? Ṣebí aposteli ni mí? Ṣebí mo ti rí Jesu Oluwa wa sójú? Ṣebí àyọrísí iṣẹ́ mi ninu Oluwa ni yín? 2…

KỌRINTI KINNI 10

Ìkìlọ̀ Nípa Ìbọ̀rìṣà 1 Ẹ̀yin ará, ẹ má gbàgbé pé gbogbo àwọn baba wa ni wọ́n wà lábẹ́ ìkùukùu. Gbogbo wọn ni wọ́n la òkun kọjá. 2 Gbogbo wọn ni…

KỌRINTI KINNI 11

1 Ẹ máa fara wé mi bí èmi náà tí ń fara wé Kristi. Obinrin Níláti Bo Orí ninu Ìsìn 2 Mo yìn yín nítorí pé ẹ̀ ń ranti mi…

KỌRINTI KINNI 12

Àwọn Ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ 1 Ẹ̀yin ará, n kò fẹ́ kí nǹkan nípa ẹ̀bùn Ẹ̀mí Mímọ́ ṣókùnkùn si yín. 2 Ẹ mọ̀ pé nígbà tí ẹ jẹ́ aláìmọ Ọlọrun, ẹ̀…

KỌRINTI KINNI 13

Ìfẹ́ 1 Ǹ báà lè sọ oríṣìíríṣìí èdè tí eniyan ń fọ̀, kódà kí n tún lè sọ ti àwọn angẹli, bí n kò bá ní ìfẹ́, bí idẹ tí…

KỌRINTI KINNI 14

Ẹ̀bùn Èdè Àjèjì ati Ti Ìsọtẹ́lẹ̀ 1 Ẹ máa lépa ìfẹ́. Ṣugbọn ẹ tún máa tiraka láti ní Ẹ̀mí Mímọ́, pàápàá jùlọ, ẹ̀bùn ìsọtẹ́lẹ̀. 2 Nítorí ẹni tí ó bá…

KỌRINTI KINNI 15

Ajinde Kristi 1 Ará, mo fẹ́ ran yín létí ọ̀rọ̀ ìyìn rere tí mo fi waasu fun yín, tí ẹ gbà, tí ẹ sì bá dúró. 2 Nípa ìyìn rere…

KỌRINTI KINNI 16

Ìtọrẹ Onigbagbọ 1 Nípa ti ìtọrẹ tí ẹ̀ ń ṣe fún àwọn eniyan Ọlọrun, bí mo ti ṣe ètò pẹlu àwọn ìjọ Galatia, bẹ́ẹ̀ gan-an ni kí ẹ̀yin náà máa…

KỌRINTI KEJI 1

Ìkíni 1 Èmi Paulu, aposteli Kristi Jesu nípasẹ̀ ìfẹ́ Ọlọrun, ati Timoti, arakunrin wa, ni à ń kọ ìwé yìí sí Ìjọ Ọlọrun tí ó wà ní Kọrinti ati sí…

KỌRINTI KEJI 2

1 Nítorí náà, mo pinnu pé n kò tún fẹ́ kí wíwá tí mo bá wá sọ́dọ̀ yín jẹ́ ti ìbànújẹ́ mọ́. 2 Bí mo bá bà yín ninu jẹ́,…