KỌRINTI KEJI 3

Òjíṣẹ́ Majẹmu Titun 1 Ṣé a óo ṣẹ̀ṣẹ̀ tún bẹ̀rẹ̀ láti máa ṣe àpèjúwe ara wa ni; àbí a nílò láti mú ìwé ẹ̀rí tọ̀ yín wá tí yóo sọ…

KỌRINTI KEJI 4

Ìṣúra ti Ẹ̀mí ninu ìkòkò Amọ̀ 1 Nítorí èyí, níwọ̀n ìgbà tí ó wu Ọlọrun ninu àánú rẹ̀ láti fi iṣẹ́ yìí fún wa ṣe, ọkàn wa kò rẹ̀wẹ̀sì. 2…

KỌRINTI KEJI 5

1 Nítorí a mọ̀ pé bí àgọ́ ara tí a fi ṣe ilé ní ayé yìí bá wó, a ní ilé kan lọ́dọ̀ Ọlọrun, tí a kò fi ọwọ́ kọ́,…

KỌRINTI KEJI 6

1 Gẹ́gẹ́ bí alábàáṣiṣẹ́pọ̀, à ń bẹ̀ yín pé kí ẹ má ṣe jẹ́ kí gbígbà tí ẹ gba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun jẹ́ lásán. 2 Nítorí Ọlọrun sọ pé, “Mo gbọ́…

KỌRINTI KEJI 7

1 Nítorí náà, ẹ̀yin àyànfẹ́, nígbà tí ẹ ti ní àwọn ìlérí yìí, ẹ wẹ gbogbo ìdọ̀tí kúrò ní ara ati ẹ̀mí yín. Ẹ ya ara yín sí mímọ́ patapata…

KỌRINTI KEJI 8

Àwọn Onigbagbọ Ará Masedonia Lawọ́ 1 Ẹ̀yin ará, a fẹ́ kí ẹ mọ ohun tí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọrun ti ṣe láàrin àwọn ìjọ Masedonia. 2 Wọ́n ní ọpọlọpọ ìdánwò nípa ìpọ́njú….

KỌRINTI KEJI 9

Ọrẹ fún Àwọn Onigbagbọ 1 Nípa ti ìrànlọ́wọ́ fún àwọn onigbagbọ, kò nílò pé kí n tún kọ ìwé si yín mọ́. 2 Nítorí mo mọ àníyàn yín, mo sì…

KỌRINTI KEJI 10

Paulu Gbèjà Ara Rẹ̀ 1 Èmi Paulu fi ìrẹ̀lẹ̀ Kristi ati àánú rẹ̀ bẹ̀ yín, èmi tí ẹ̀ ń sọ pé nígbà tí mo bá wà lọ́dọ̀ yín mo jẹ́…

KỌRINTI KEJI 11

Paulu ati Àwọn Aposteli Èké 1 Ẹ jọ̀wọ́, ẹ gbà mí láyè kí n sọ̀rọ̀ díẹ̀ bí aṣiwèrè. Ẹ gbà mí láyè. 2 Mò ń jowú nítorí yín, bí Ọlọrun…

KỌRINTI KEJI 12

Àwọn Ìran Tí Paulu Rí 1 Ó yẹ kí n fọ́nnu. Rere kan kò ti ibẹ̀ wá, sibẹ n óo sọ ti ìran ati ìfarahàn Oluwa. 2 Mo mọ ọkunrin…