HEBERU 8

Olórí Alufaa ti Majẹmu Titun 1 Kókó ohun tí à ń sọ nìyí, pé a ní irú Olórí Alufaa báyìí, ẹni tí ó jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún ìtẹ́ ọlá ńlá…

HEBERU 9

Ilé Ìsìn Ti Ayé ati Ti Ọ̀run 1 Majẹmu àkọ́kọ́ ni àwọn ètò ìsìn ati ilé ìsìn bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ti ayé ni. 2 Nítorí wọ́n pa àgọ́…

HEBERU 10

1 Nítorí Òfin Mose jẹ́ òjìji àwọn ohun rere tí ń bọ̀, kì í ṣe àwòrán wọn gan-an. Òfin ṣe ìlànà nípa irú ẹbọ kan náà tí àwọn eniyan yóo…

HEBERU 11

Igbagbọ 1 Igbagbọ ni ìdánilójú ohun tí à ń retí, ẹ̀rí tí ó dájú nípa àwọn ohun tí a kò rí. 2 Igbagbọ ni àwọn àgbà àtijọ́ ní, tí wọ́n…

HEBERU 12

Ìtọ́ni ti Oluwa 1 Níwọ̀n ìgbà tí a ní àwọn tí wọn ń jẹ́rìí sí agbára igbagbọ, tí wọ́n yí wa ká bí awọsanma báyìí, ẹ jẹ́ kí á pa…

HEBERU 13

Ìsìn Tí Ó Wu Ọlọrun 1 Àwọn onigbagbọ níláti fẹ́ràn ara wọn. 2 Ẹ má gbàgbé láti máa ṣe àlejò nítorí nípa àlejò ṣíṣe àwọn ẹlòmíràn ti ṣe àwọn angẹli…

JAKỌBU 1

Ìkíni 1 Èmi Jakọbu, iranṣẹ Ọlọrun, ati ti Oluwa wa, Jesu Kristi, ni ó ń kọ ìwé yìí sí àwọn ẹ̀yà mejila tí ó fọ́nká gbogbo ayé. Alaafia fun yín!…

JAKỌBU 2

Ẹ Má Ṣe Ojuṣaaju 1 Ẹ̀yin ará mi, níwọ̀n ìgbà tí ẹ ní igbagbọ ninu Oluwa wa, Jesu Kristi, Oluwa tí ó lógo, ẹ má máa ṣe ojuṣaaju. 2 Bí…

JAKỌBU 3

Ahọ́n 1 Ẹ̀yin ará mi, kí ọpọlọpọ yín má máa jìjàdù láti jẹ́ olùkọ́ni, kí ẹ mọ̀ pé ìdájọ́ ti àwa olùkọ́ni yóo le. 2 Nítorí gbogbo wa ni à…

JAKỌBU 4

Bíbá Ayé Rẹ́ 1 Níbo ni ogun ti ń wá? Níbo ni ìjà sì ti ń wá sáàrin yín? Ṣebí nípa ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ yín tí ó ń jagun ninu àwọn ẹ̀yà…