JẸNẸSISI 11

Ilé Ìṣọ́ Babeli 1 Nígbà kan èdè kan ṣoṣo ni ó wà láyé, ọ̀rọ̀ bíi mélòó kan ni gbogbo wọ́n sì ń lò. 2 Bí àwọn eniyan ṣe ń ṣí…

JẸNẸSISI 12

Ọlọrun Pe Abramu 1 Ní ọjọ́ kan, Ọlọrun sọ fún Abramu pé, “Jáde kúrò ní ilẹ̀ rẹ, láàrin àwọn ìbátan rẹ, ati kúrò ní ilé baba rẹ lọ sí ilẹ̀…

JẸNẸSISI 13

Abramu ati Lọti Pínyà 1 Bẹ́ẹ̀ ni Abramu ṣe jáde kúrò ní Ijipti, ó pada lọ sí Nẹgẹbu pẹlu aya rẹ̀, ati Lọti ati ohun gbogbo tí ó ní. 2…

JẸNẸSISI 14

Abramu Gba Lọti sílẹ̀ 1 Nígbà kan, àwọn ọba mẹrin kan: Amrafeli, ọba Babiloni, Arioku, ọba Elasari, Kedorilaomeri, ọba Elamu, ati Tidali, ọba Goiimu, 2 gbógun ti Bera, ọba Sodomu,…

JẸNẸSISI 15

Majẹmu Ọlọrun pẹlu Abramu 1 Lẹ́yìn nǹkan wọnyi, OLUWA bá Abramu sọ̀rọ̀ lójú ìran, ó ní, “Má bẹ̀rù Abramu, n óo dáàbò bò ọ́, èrè rẹ yóo sì pọ̀ pupọ.”…

JẸNẸSISI 16

Hagari ati Iṣimaeli 1 Sarai, aya Abramu, kò bímọ fún un. Ṣugbọn ó ní ẹrubinrin ará Ijipti kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hagari. 2 Ní ọjọ́ kan, Sarai pe…

JẸNẸSISI 17

Ilà Abẹ́ Kíkọ, Àmì Majẹmu Ọlọrun 1 Nígbà tí Abramu di ẹni ọdún mọkandinlọgọrun-un, OLUWA farahàn án, ó sọ fún un pé, “Èmi ni Ọlọrun Olodumare, máa gbọ́ tèmi, kí…

JẸNẸSISI 18

Ọlọrun Ṣèlérí Ọmọkunrin Kan fún Abrahamu 1 Ní ọ̀sán gangan ọjọ́ kan, OLUWA fara han Abrahamu bí ó ti jókòó ní ẹnu ọ̀nà àgọ́ rẹ̀, lẹ́bàá igi Oaku ti Mamure….

JẸNẸSISI 19

Ìwà Ẹ̀ṣẹ̀ Sodomu 1 Ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà ni àwọn angẹli meji náà dé ìlú Sodomu, Lọti sì jókòó ní ẹnubodè ìlú náà. Bí ó ti rí wọn, ó dìde…

JẸNẸSISI 20

Abrahamu ati Abimeleki 1 Láti ibẹ̀ ni Abrahamu ti lọ sí agbègbè Nẹgẹbu, ó sì ń gbé Gerari, ní ààrin Kadeṣi ati Ṣuri. 2 Abrahamu sọ fún àwọn ará Gerari…