ÀWỌN ADÁJỌ́ 10

Tola 1 Lẹ́yìn tí Abimeleki kú, Tola ọmọ Pua, ọmọ Dodo, láti inú ẹ̀yà Isakari ni ó dìde tí ó sì gba Israẹli kalẹ̀. Ìlú Ṣamiri tí ó wà ní…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 11

1 Jẹfuta ará Gileadi jẹ́ akikanju jagunjagun, ṣugbọn ọmọ aṣẹ́wó ni; Gileadi ni baba rẹ̀. 2 Ṣugbọn iyawo Gileadi gan-an bí àwọn ọmọkunrin mìíràn. Nígbà tí àwọn ọmọkunrin wọnyi dàgbà,…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 12

Jẹfuta ati Àwọn Ará Efuraimu 1 Àwọn ọmọ Efuraimu múra ogun, wọ́n ré odò Jọdani kọjá lọ sí Safoni. Wọ́n bi Jẹfuta léèrè pé, “Kí ló dé tí o fi…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 13

Ìbí Samsoni 1 Àwọn ọmọ Israẹli tún ṣe ohun tí ó burú lójú OLUWA, OLUWA sì fi wọ́n lé àwọn ará Filistia lọ́wọ́. Wọ́n sin àwọn ará Filistia fún ogoji…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 14

Samsoni ati Ọmọbinrin Kan, Ará Timna 1 Samsoni lọ sí Timna, ó rí ọ̀kan ninu àwọn ọmọbinrin ará Filistia níbẹ̀. 2 Ó pada wálé wá sọ fún baba ati ìyá…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 15

1 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ní àkókò ìkórè ọkà, Samsoni mú ọmọ ewúrẹ́ kan, ó lọ bẹ iyawo rẹ̀ wò. Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó ní, “Mo fẹ́ wọlé lọ…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 16

Samsoni ní Ìlú Gasa 1 Ní ọjọ́ kan, Samsoni lọ sí ìlú Gasa, ó rí obinrin aṣẹ́wó kan níbẹ̀, ó bá wọlé tọ̀ ọ́ lọ. 2 Àwọn kan bá lọ…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 17

Ère Mika 1 Ọkunrin kan wà ní agbègbè olókè ti Efuraimu tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. 2 Ó sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Wọ́n gbé ẹẹdẹgbẹfa (1,100) owó fadaka…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 18

Mika ati Ẹ̀yà Dani 1 Ní àkókò kan, kò sí ọba ní ilẹ̀ Israẹli, ati pé, ní àkókò náà, àwọn ẹ̀yà Dani ń wá ilẹ̀ tí wọn yóo gbà, tí…

ÀWỌN ADÁJỌ́ 19

Ọmọ Lefi Kan ati Obinrin Rẹ̀ 1 Ní àkókò tí kò sí ọba ní Israẹli, ọmọ Lefi kan ń gbé apá ibìkan tí ó jìnnà ní agbègbè olókè ti Efuraimu….