SAMUẸLI KINNI 15

Àwọn Ọmọ Israẹli Bá Àwọn Ará Amaleki Jagun 1 Samuẹli sọ fún Saulu pé, “OLUWA rán mi láti fi òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli, eniyan rẹ̀. Nisinsinyii gbọ́…

SAMUẸLI KINNI 16

Wọ́n Fi Àmì Òróró Yan Dafidi lọ́ba 1 OLUWA wí fún Samuẹli pé, “Ìgbà wo ni o fẹ́ káàánú lórí Saulu dà? Ṣebí o mọ̀ pé mo ti kọ̀ ọ́…

SAMUẸLI KINNI 17

Goliati Pe Àwọn Ọmọ Israẹli Níjà 1 Àwọn ọmọ ogun Filistini kó ara wọn jọ sí Soko, ìlú kan ní ilẹ̀ Juda láti bá Israẹli jagun. Wọ́n pa ibùdó wọn…

SAMUẸLI KINNI 18

1 Lẹ́yìn tí Dafidi ati Saulu parí ọ̀rọ̀ wọn, ọkàn Jonatani, ọmọ Saulu fà mọ́ Dafidi lọpọlọpọ ó sì fẹ́ràn rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀mí ara rẹ̀. 2 Saulu gba Dafidi…

SAMUẸLI KINNI 19

Saulu Fẹ́ Pa Dafidi 1 Saulu sọ fún ọmọ rẹ̀ Jonatani ati gbogbo àwọn iranṣẹ rẹ̀ pé kí wọ́n pa Dafidi. Ṣugbọn Jonatani fẹ́ràn Dafidi lọpọlọpọ. 2 Ó sì sọ…

SAMUẸLI KINNI 20

Jonatani Ran Dafidi lọ́wọ́ 1 Dafidi sá kúrò ní Naioti, ní Rama, lọ sọ́dọ̀ Jonatani, ó sì bi í pé, “Kí ni mo ṣe? Ìwà burúkú wo ni mo hù?…

SAMUẸLI KINNI 21

Dafidi Sá fún Saulu 1 Dafidi lọ sọ́dọ̀ Ahimeleki alufaa, ní Nobu. Ahimeleki sì jáde pẹlu ìbẹ̀rù láti pàdé rẹ̀, ó sì bi í pé, “Ṣé kò sí nǹkan tí…

SAMUẸLI KINNI 22

Saulu Pa Àwọn Alufaa 1 Dafidi sá kúrò ní ìlú Gati, lọ sinu ihò òkúta kan lẹ́bàá Adulamu. Nígbà tí àwọn arakunrin rẹ̀ ati ìdílé baba rẹ̀ gbọ́, wọ́n wá…

SAMUẸLI KINNI 23

Dafidi Gba Ìlú Keila Sílẹ̀ 1 Nígbà tí Dafidi gbọ́ pé àwọn ará Filistia ń gbógun ti àwọn ará Keila, wọ́n sì ń jí ọkà wọn kó ní ibi ìpakà,…

SAMUẸLI KINNI 24

Dafidi Dá Ẹ̀mí Saulu Sí 1 Nígbà tí Saulu bá àwọn ará Filistia jagun tán, wọ́n sọ fún un pé Dafidi wà ní aṣálẹ̀ Engedi. 2 Saulu mú ẹgbẹẹdogun (3,000)…