KRONIKA KEJI 34

Josaya, Ọba Juda 1 Ọmọ ọdún mẹjọ ni Josaya nígbà tí ó jọba, ó sì wà lórí oyè ní Jerusalẹmu fún ọdún mọkanlelọgbọn. 2 Ó ṣe ohun tí ó dára…

KRONIKA KEJI 35

Josaya Pa Àjọ Ìrékọjá Mọ́ 1 Josaya ṣe Àjọ Ìrékọjá fún OLUWA ní Jerusalẹmu. Ní ọjọ́ kẹrinla, oṣù kinni ni wọ́n pa ọ̀dọ́ aguntan Àjọ Ìrékọjá. 2 Ó yan àwọn…

KRONIKA KEJI 36

Joahasi, ọba Juda 1 Àwọn ọmọ ilẹ̀ Juda bá fi Joahasi, ọmọ Josaya, jọba ní Jerusalẹmu lẹ́yìn baba rẹ̀. 2 Joahasi jẹ́ ẹni ọdún mẹtalelogun nígbà tí ó jọba, ó…

ẸSIRA 1

Kirusi Ọba Pàṣẹ pé kí Àwọn Juu Pada 1 Ní ọdún kinni ìjọba Kirusi, ọba Pasia, kí àsọtẹ́lẹ̀ láti ẹnu wolii Jeremaya lè ṣẹ, OLUWA fi sí Kirusi ọba lọ́kàn…

ẸSIRA 2

Àwọn tí Wọ́n Pada ti Oko Ẹrú Dé 1 Àwọn ọmọ Juda wọnyi ni wọ́n pada dé láti oko ẹrú ní Babiloni, níbi tí Nebukadinesari, ọba Babiloni, kó wọn lẹ́rú…

ẸSIRA 3

Wọ́n tún Bẹ̀rẹ̀ Ìjọ́sìn 1 Ní oṣù keje tí àwọn ọmọ Israẹli ti pada sí ìlú wọn, gbogbo wọn péjọ sí Jerusalẹmu. 2 Jeṣua, ọmọ Josadaki pẹlu àwọn alufaa ẹgbẹ́…

ẸSIRA 4

Àtakò Sí Títún Ilé Ọlọrun Kọ́ 1 Nígbà ti àwọn ọ̀tá Juda ati ti Bẹnjamini gbọ́ pé àwọn tí wọ́n ti ìgbèkùn dé ti bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ ilé OLUWA Ọlọrun…

ẸSIRA 5

Iṣẹ́ Kíkọ́ Tẹmpili Tún Bẹ̀rẹ̀ 1 Wolii Hagai ati wolii Sakaraya, ọmọ Ido, bẹ̀rẹ̀ sí sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún àwọn Juu tí wọ́n wà ni Juda ati Jerusalẹmu ní orúkọ Ọlọrun…

ẸSIRA 6

Wọ́n Rí Àkọsílẹ̀ Àṣẹ tí Kirusi Ọba Pa 1 Dariusi ọba pàṣẹ pé kí wọ́n wádìí fínnífínní ninu àwọn ìwé àkọsílẹ̀ tí ó wà ní ààfin, ní ilẹ̀ Babiloni. 2…

ẸSIRA 7

Ẹsira Dé sí Jerusalẹmu 1 Lẹ́yìn náà, ní àkókò ìjọba Atasasesi, ọba Pasia, ọkunrin kan wà, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹsira, ọmọ Seraaya, ọmọ Asaraya, ọmọ Hilikaya, 2 ọmọ Ṣalumu,…