ẸSITA 5

Ẹsita Pe Ọba ati Hamani sí Àsè 1 Ní ọjọ́ kẹta, Ẹsita wọ aṣọ oyè rẹ̀, ó dúró ní àgbàlá ààfin ọba, ó kọjú sí gbọ̀ngàn ọba. Ọba jókòó lórí…

ẸSITA 6

Ọba Dá Modekai Lọ́lá 1 Ní òru ọjọ́ náà, ọba kò lè sùn. Ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n gbé ìwé àkọsílẹ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìjọba rẹ̀ wá, kí wọ́n sì…

ẸSITA 7

1 Ọba ati Hamani lọ bá Ayaba Ẹsita jẹ àsè. 2 Ní ọjọ́ keji, bí wọ́n ti ń mu ọtí, ọba tún bi Ẹsita pé, “Ẹsita, Ayaba, kí ni ẹ̀bẹ̀…

ẸSITA 8

Wọ́n fún Àwọn Juu Láṣẹ láti Bá Àwọn Ọ̀tá Wọn Jà 1 Ní ọjọ́ náà gan-an ni ọba Ahasu-erusi fún Ẹsita Ayaba ní ilé Hamani, ọ̀tá àwọn Juu. Ẹsita wá…

ẸSITA 9

Àwọn Juu Pa Àwọn Ọ̀tá Wọn Run 1 Ní ọjọ́ kẹtala oṣù Adari tíí ṣe oṣù kejila, nígbà tí wọ́n ń múra láti ṣe ohun tí òfin ọba wí, ní…

ẸSITA 10

Títóbi Ahasu-erusi ati Modekai 1 Ọba Ahasu-erusi pàṣẹ pé kí àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n jìnnà ati àwọn tí wọn ń gbé etíkun máa san owó orí. 2 Gbogbo iṣẹ́ agbára…

JOBU 1

Satani Dán Jobu Wò 1 Ọkunrin kan wà tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jobu; ó ń gbé ilẹ̀ Usi, ó jẹ́ olódodo ati olóòótọ́ eniyan, ó bẹ̀rù Ọlọrun, ó sì…

JOBU 2

Satani Tún Dán Jobu Wò 1 Nígbà tí ó tún yá tí àwọn ọmọ Ọlọrun wá farahàn níwájú OLUWA, Satani náà wà láàrin wọn. 2 OLUWA tún bi Satani pé,…

JOBU 3

Jobu Ráhùn sí Ọlọrun 1 Nígbà tí ó yá, Jobu bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀, ó fi ọjọ́ ìbí ara rẹ̀ bú. 2 Ó ní: 3 “Ègún ni fún ọjọ́ tí wọ́n…

JOBU 4

Ìfọ̀rọ̀wérọ̀ Kinni 1 Nígbà náà ni Elifasi, ará Temani, dá Jobu lóhùn, ó ní: 2 “Bí eniyan bá bá ọ sọ̀rọ̀, ṣé kò ní bí ọ ninu? Àbí eniyan ha…