JOBU 15
Ìfọ̀rọ̀wérọ̀ Keji 1 Elifasi ará Temani bá dáhùn pé, 2 “Ṣé ọlọ́gbọ́n a máa fọ èsì tí kò mọ́gbọ́n lọ́wọ́? Kí ó dàbí àgbá òfìfo? 3 Kí ó máa jiyàn…
Ìfọ̀rọ̀wérọ̀ Keji 1 Elifasi ará Temani bá dáhùn pé, 2 “Ṣé ọlọ́gbọ́n a máa fọ èsì tí kò mọ́gbọ́n lọ́wọ́? Kí ó dàbí àgbá òfìfo? 3 Kí ó máa jiyàn…
1 Jobu bá dáhùn pé, 2 “Èmi náà ti gbọ́ irú nǹkan wọnyi rí, ọlọ́rọ̀ ìtùnú kòbákùngbé ni gbogbo yín. 3 Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ asán tí ẹ̀ ń sọ yìí tilẹ̀…
1 “Ọkàn mi bàjẹ́, ọjọ́ ayé mi ti dópin, ibojì sì ń dúró dè mí. 2 Dájúdájú àwọn ẹlẹ́yà yí mi káàkiri, wọ́n ń fi mí ṣe yẹ̀yẹ́ lojukooju. 3…
1 Bilidadi ará Ṣuha bá tún dáhùn pé, 2 “Ìgbàwo ni o óo sinmi ẹjọ́ tí ò ń tò yìí? Ohun tí a tí ń bá ọ sọ ni kí…
1 Jobu bá dáhùn, ó ní, 2 “Ẹ óo ti ni mí lára pẹ́ tó, tí ẹ óo máa fi ọ̀rọ̀ yín bà mí ninu jẹ́? 3 Ẹ kẹ́gàn mi…
1 Sofari, ará Naama bá dáhùn pé, 2 “Lọ́kàn mi, mo fẹ́ fèsì sí ọ̀rọ̀ rẹ, ara sì ń wá mi, bí ẹni pé kí n dá ọ lóhùn. 3…
1 Jobu dáhùn pé, 2 “Ẹ fetí sí ọ̀rọ̀ mi dáradára, kí ẹ sì jẹ́ kí ó jẹ́ ìtùnú fun yín. 3 Ẹ farabalẹ̀, kí ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, lẹ́yìn…
ÌFỌ̀RỌ̀WÉRỌ̀ KẸTA 1 Elifasi ará Temani bá dáhùn pé, 2 “Ǹjẹ́ eniyan lè wúlò fún Ọlọrun? Nítòótọ́, bí eniyan tilẹ̀ jẹ́ ọlọ́gbọ́n, ara rẹ̀ ni ó wúlò fún. 3 Ǹjẹ́…
1 Nígbà náà ni Jobu dáhùn pé, 2 “Lónìí, ìráhùn mi tún kún fún ẹ̀dùn, ọwọ́ Ọlọrun ń le lára mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mò ń kérora. 3…
1 “Kí ló dé tí Olodumare kò fi yan ọjọ́ ìdájọ́, kí àwọn tí wọ́n mọ̀ ọ́n sì rí ọjọ́ náà? 2 “Àwọn eniyan a máa hú òkúta ààlà kúrò,…