JOBU 25
1 Bilidadi ará Ṣuha bá dáhùn pé, 2 “Ọlọrun ni ọba, òun ló sì tó bẹ̀rù, ó ń ṣe àkóso alaafia lọ́run. 3 Ta ló lè ka àwọn ọmọ ogun…
1 Bilidadi ará Ṣuha bá dáhùn pé, 2 “Ọlọrun ni ọba, òun ló sì tó bẹ̀rù, ó ń ṣe àkóso alaafia lọ́run. 3 Ta ló lè ka àwọn ọmọ ogun…
1 Jobu bá dáhùn pé, 2 “Ìrànlọ́wọ́ wo ni ẹ ti ṣe fún àwọn tí wọn kò lágbára? Aláìlera wo ni ẹ ti gbàlà? 3 Ìmọ̀ràn wo ni ẹ ti…
1 Jobu tún dáhùn pé, 2 “Mo fi Ọlọrun tí ó gba ẹ̀tọ́ mi búra, mo fi Olodumare tí ó mú kí ọkàn mi bàjẹ́ ṣẹ̀rí, 3 níwọ̀n ìgbà tí…
Ọ̀rọ̀ Ìyìn Nípa Ọgbọ́n 1 “Dájúdájú, ibìkan wà tí wọ́n ti ń wa fadaka, ibìkan sì wà tí wọ́n ti ń yọ́ wúrà. 2 Inú ilẹ̀ ni a ti ń…
Ìparí Ọ̀rọ̀ Jobu 1 Jobu tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ lọ báyìí pé, 2 “Ìbá jẹ́ tún rí fún mi, bí ìgbà àtijọ́, nígbà tí Ọlọrun ń tọ́jú mi; 3…
1 “Ṣugbọn nisinsinyii àwọn tí wọ́n kéré sí mi ń fi mí ṣe ẹlẹ́yà, àwọn tí baba wọn kò tó fi wé àwọn ajá tí ń ṣọ́ agbo ẹran mi….
1 “Mo ti bá ojú mi dá majẹmu; n óo ṣe wá máa wo wundia? 2 Kí ni yóo jẹ́ ìpín mi lọ́dọ̀ Ọlọrun lókè? Kí ni ogún mi lọ́dọ̀…
Ọ̀rọ̀ Elihu 1 Àwọn ọkunrin mẹtẹẹta náà kò dá Jobu lóhùn mọ́, nítorí pé ó jẹ́ olódodo lójú ara rẹ̀. 2 Elihu, ọmọ Barakeli, ará Busi, ní ìdílé Ramu bá…
1 “Jobu, tẹ́tí sílẹ̀ nisinsinyii kí o gbọ́ ọ̀rọ̀ mi. 2 Wò ó! Mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ sì pọ̀ tí mo fẹ́ sọ. 3 Òtítọ́ inú ni mo…
1 Elihu tún ń bá ọ̀rọ̀ rẹ̀ bọ̀, ó ní, 2 “Ẹ gbọ́rọ̀ mi, ẹ̀yin ọlọ́gbọ́n, ẹ tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin tí ẹ ní ìmọ̀, 3 nítorí bí ahọ́n ti…