ORIN DAFIDI 73

Ìdájọ́ Òdodo Ọlọrun 1 Nítòótọ́ Ọlọrun ṣeun fún Israẹli, ó ṣeun fún àwọn tí ọkàn wọn mọ́. 2 Ṣugbọn, ní tèmi, mo fẹ́rẹ̀ yọ̀ ṣubú, ẹsẹ̀ mi fẹ́rẹ̀ tàsé. 3…

ORIN DAFIDI 74

Ranti Wa, OLUWA 1 Ọlọrun, kí ló dé tí o fi ta wá nù títí ayé? Kí ló dé tí inú rẹ fi ń ru sí àwa aguntan pápá rẹ?…

ORIN DAFIDI 75

Ọlọrun Onídàájọ́ 1 A dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Ọlọrun; a dúpẹ́. À ń kéde orúkọ rẹ, a sì ń ròyìn iṣẹ́ ribiribi tí o ṣe. 2 OLUWA ní, “Nígbà tí àkókò…

ORIN DAFIDI 76

Ọlọrun Ajàṣẹ́gun 1 Àwọn ará Juda mọ Ọlọrun, orúkọ rẹ̀ sì lọ́wọ̀ ní Israẹli. 2 Ilé rẹ̀ wà ní Salẹmu, ibùgbé rẹ̀ wà ní Sioni. 3 Níbẹ̀ ni ó ti…

ORIN DAFIDI 77

Ìtùnú ní Àkókò Ìpọ́njú 1 Mo ké pe Ọlọrun fún ìrànlọ́wọ́, mo kígbe pe Ọlọrun kí ó lè gbọ́ tèmi. 2 Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi, mo wá OLUWA; ní òru,…

ORIN DAFIDI 78

Ọlọrun ati Àwọn Eniyan Rẹ̀ 1 Ẹ̀yin eniyan mi, ẹ dẹtí sí ẹ̀kọ́ mi; ẹ tẹ́tí si ọ̀rọ̀ ẹnu mi. 2 N óo la ẹnu mi tòwe-tòwe; n óo fa…

ORIN DAFIDI 79

Adura Ìdáǹdè Orílẹ̀-Èdè 1 Ọlọrun, àwọn orílẹ̀-èdè abọ̀rìṣà ti wọ inú ilẹ̀ ìní rẹ; wọ́n ti ba ilé mímọ́ rẹ jẹ́; wọ́n sì ti sọ Jerusalẹmu di ahoro. 2 Wọ́n…

ORIN DAFIDI 80

Fi Ojurere Wò Wá 1 Dẹtí sílẹ̀, ìwọ olùṣọ́-aguntan Israẹli, Ìwọ tí ò ń tọ́jú àwọn ọmọ Josẹfu bí agbo ẹran. Ìwọ tí o gúnwà láàrin àwọn kerubu, yọ bí…

ORIN DAFIDI 81

Orin fún Àkókò Àsè 1 Ẹ kọ orin sókè sí Ọlọrun, agbára wa; ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọrun Jakọbu. 2 Ẹ dárin, ẹ lu samba, ẹ ta hapu dídùn…

ORIN DAFIDI 82

Ọlọrun, Ọba Àwọn Ọba 1 Ọlọrun ti jókòó ní ààyè rẹ̀ ninu ìgbìmọ̀ ọ̀run; ó sì ń ṣe ìdájọ́ láàrin àwọn ẹ̀dá ọ̀run: 2 “Yóo ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin…