AISAYA 42

Iranṣẹ Ọlọrun 1 OLUWA ní, “Wo iranṣẹ mi, ẹni tí mo gbéró, àyànfẹ́ mi, ẹni tí inú mi dùn sí. Mo ti jẹ́ kí ẹ̀mí mi bà lé e, yóo…

AISAYA 43

OLUWA Ṣe Ìlérí láti Gba Àwọn Eniyan Rẹ̀ Là 1 Ṣugbọn nisinsinyii, Jakọbu, gbọ́ nǹkan tí OLUWA ẹlẹ́dàá rẹ wí, Israẹli, gbọ́ ohun tí ẹni tí ó dá ọ sọ….

AISAYA 44

Ọlọrun kanṣoṣo ni OLUWA 1 OLUWA ní: “Ṣugbọn nisinsinyii, ẹ̀yin ọmọ Jakọbu iranṣẹ mi ẹ̀yin ọmọ Israẹli, àyànfẹ́ mi. 2 Ẹ gbọ́ ohun tí OLUWA, Ẹlẹ́dàá yín wí, ẹni tí…

AISAYA 45

OLUWA Yan Kirusi 1 Ohun tí OLUWA sọ fún kirusi, ẹni tí ó fi àmì òróró yàn nìyí: Ẹni tí OLUWA di ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ mú, tí ó lò, láti…

AISAYA 46

1 “Oriṣa Bẹli tẹríba, oriṣa Nebo doríkodò. Orí àwọn ẹran ọ̀sìn ati mààlúù ni àwọn oriṣa wọn wà. Àwọn nǹkan tí ẹ̀ ń rù kiri wá di ẹrù, tí àwọn…

AISAYA 47

Ìdájọ́ lórí Babiloni 1 Sọ̀kalẹ̀ kí o jókòó ninu eruku, ìwọ Babiloni. Jókòó ní ilẹ̀ẹ́lẹ̀, láìsí ìtẹ́-ọba, ìwọ ọmọbinrin Kalidea. A kò ní pè ọ́ ní ẹlẹgẹ́ ati aláfẹ́ mọ́….

AISAYA 48

Ọlọrun ni OLUWA Ọjọ́ Iwájú 1 Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀yin ará ilé Jakọbu, ẹ̀yin tí à ń fi orúkọ Israẹli pè, ọmọ bíbí inú Juda, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń…

AISAYA 49

Israẹli, Ìmọ́lẹ̀ fún Ayé 1 Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ilẹ̀ etí òkun. Ẹ fetí sílẹ̀ sí ọ̀rọ̀ mi, ẹ̀yin ará ilẹ̀ òkèèrè, láti inú oyún ni OLUWA ti pè mí, láti…

AISAYA 50

1 OLUWA ní: OLUWA ní: “Ìwé ìkọ̀sílẹ̀ tí mo fi kọ àwọn eniyan mi sílẹ̀ dà? Ta ni mo tà yín fún, tí mo jẹ lówó? Ẹ wò ó! Nítorí…

AISAYA 51

Ọ̀rọ̀ Ìtùnú fún Jerusalẹmu 1 “Ẹ gbọ́ ẹ̀yin tí ẹ̀ ń sáré ìdáǹdè, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń wá OLUWA, ẹ wo àpáta tí a mú lára rẹ̀, tí a fi…