JEREMAYA 16

Ìfẹ́ OLUWA ní Ìgbésí Ayé Jeremaya 1 OLUWA tún bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “O kò gbọdọ̀ fẹ́ iyawo tabi kí o bímọ ní ibí yìí. 3 Nítorí ohun…

JEREMAYA 17

Ẹ̀ṣẹ̀ ati Ìjìyà Juda 1 OLUWA ní, “Gègé irin ni a fi kọ ẹ̀ṣẹ̀ Juda sílẹ̀ gègé òkúta dayamọndi ni a sì fi kọ ọ́ sí ọkàn yín, ati sí…

JEREMAYA 18

Jeremaya nílé Amọ̀kòkò 1 OLUWA bá Jeremaya sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “Dìde, lọ sí ilé amọ̀kòkò, níbẹ̀ ni óo ti gbọ́ ọ̀rọ̀ tí mo fẹ́ bá ọ sọ.” 3 Mo…

JEREMAYA 19

Ìgò Amọ̀ Tí Ó Fọ́ 1 OLUWA ní kí n lọ ra ìgò amọ̀ kan, kí n mú díẹ̀ ninu àwọn àgbààgbà ìlú ati àwọn bíi mélòó kan ninu àwọn…

JEREMAYA 20

Ìjà láàrin Jeremaya ati Paṣuri Alufaa 1 Nígbà tí Paṣuri alufaa, ọmọ Imeri, tí ó jẹ́ olórí àwọn olùṣọ́ ilé OLUWA, gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Jeremaya ń sọ, 2 ó ní…

JEREMAYA 21

Àsọtẹ́lẹ̀ nípa Ìṣubú Jerusalẹmu 1 Ọ̀rọ̀ tí Jeremaya gbọ́ lẹ́nu OLUWA nìyí nígbà tí ọba Sedekaya rán Paṣuri, ọmọ Malikaya, ati alufaa Sefanaya, ọmọ Maaseaya, sí i; 2 tí ọba…

JEREMAYA 22

Iṣẹ́ tí Jeremaya Jẹ́ fún Ìdílé Ọba Juda 1 OLUWA sọ fún mi pé, kí n lọ sí ilé ọba Juda kí n sọ fún un níbẹ̀ pé, 2 “Gbọ́…

JEREMAYA 23

Ìrètí Ọjọ́ Iwájú 1 OLUWA ní, “Àwọn olùṣọ́-aguntan tí wọn ń tú àwọn agbo aguntan mi ká, tí wọn ń run wọ́n gbé!” 2 Nítorí náà, OLUWA, Ọlọrun Israẹli sọ…

JEREMAYA 24

Apẹ̀rẹ̀ Èso Ọ̀pọ̀tọ́ Meji 1 Lẹ́yìn tí Nebukadinesari, ọba Babiloni ti kó Jehoiakini ọba Juda, ọmọ Jehoiakimu kúrò ní ìlú Jerusalẹmu lọ sí Babiloni, pẹlu àwọn ìjòyè Juda, ati àwọn…

JEREMAYA 25

Àwọn Ọ̀tá láti Ìhà Àríwá 1 Ní ọdún kẹrin tí Jehoiakimu, ọmọ Josaya jọba ní Juda, tí ó jẹ́ ọdún kinni tí Nebukadinesari jọba Babiloni, Jeremaya wolii gbọ́ ọ̀rọ̀ OLUWA…