ẸKÚN JEREMAYA 4
Jerusalẹmu, Lẹ́yìn Ìṣubú Rẹ̀ 1 Wo bí wúrà ti dọ̀tí, tí ojúlówó wúrà sì yipada; tí àwọn òkúta Tẹmpili mímọ́ sì fọ́nká ní gbogbo ìkóríta. 2 Ẹ wo àwọn ọdọmọkunrin…
Jerusalẹmu, Lẹ́yìn Ìṣubú Rẹ̀ 1 Wo bí wúrà ti dọ̀tí, tí ojúlówó wúrà sì yipada; tí àwọn òkúta Tẹmpili mímọ́ sì fọ́nká ní gbogbo ìkóríta. 2 Ẹ wo àwọn ọdọmọkunrin…
Adura fún Àánú 1 OLUWA, ranti ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa, Ṣe akiyesi ẹ̀sín wa. 2 Àwọn ilẹ̀ àjogúnbá ẹni ẹlẹ́ni, ilé wa sì ti di ti àwọn àjèjì….
Ìtẹ́ Ọlọrun 1 Ní ọjọ́ karun-un oṣù kẹrin, ní ọgbọ̀n ọdún, èmi, Isikiẹli, ọmọ Busi, wà láàrin àwọn tí wọ́n kó ní ìgbèkùn lọ sí ilẹ̀ Babiloni. A wà lẹ́bàá…
1 Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ eniyan, dìde dúró, mo fẹ́ bá ọ sọ̀rọ̀.” 2 Bí ó ti ń bá mi sọ̀rọ̀, ẹ̀mí OLUWA wọ inú mi, ó gbé…
1 Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ Eniyan, jẹ ohun tí a fún ọ; jẹ ìwé tí a ká yìí, kí o sì lọ bá ilé Israẹli sọ̀rọ̀.” 2 Mo…
Isikiẹli Gbé Òfin Jáde lórí Ìwà Ìbàjẹ́ ní Jerusalẹmu 1 OLUWA ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, mú bulọọku kan kí o gbé e ka iwájú rẹ, kí o sì ya àwòrán…
Isikiẹli Gé Irun Rẹ̀ 1 OLUWA ní: “Ìwọ ọmọ eniyan, mú idà kan tí ó bá mú, lò ó gẹ́gẹ́ bí abẹ ìfárí, kí o fi fá orí ati irùngbọ̀n…
Ọlọrun fi Ìbọ̀rìṣà Gégùn-ún 1 OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “Ọmọ eniyan, dojú kọ àwọn òkè Israẹli kí o sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn. 3 Sọ pé, ‘Ẹ̀yin…
Òpin ti dé Tán fún Israẹli 1 OLUWA bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “Ìwọ ọmọ eniyan, ohun tí èmi OLUWA Ọlọrun sọ nípa ilẹ̀ Israẹli ni pé: òpin ti…
Ìwà Ìbọ̀rìṣà Ní Jerusalẹmu 1 Ní ọjọ́ karun-un, oṣù kẹfa ọdún kẹfa tí a ti wà ní ìgbèkùn, bí mo ti jókòó ninu ilé mi, tí àwọn àgbààgbà Juda sì…