MATIU 2

Àwọn Amòye Wá Ọmọ náà Kàn 1 Nígbà tí wọ́n bí Jesu ní Bẹtilẹhẹmu ní ilẹ̀ Judia, ní ayé Hẹrọdu ọba, àwọn amòye kan wá sí Jerusalẹmu láti ìhà ìlà…

MATIU 3

Iwaasu Johanu Onítẹ̀bọmi 1 Nígbà tí ó yá, Johanu Onítẹ̀bọmi dé, ó ń waasu ní aṣálẹ̀ Judia. 2 Ó ní, “Ẹ ronupiwada, nítorí ìjọba Ọlọrun fẹ́rẹ̀ dé.” 3 Nítorí òun…

MATIU 4

Satani Dán Jesu Wò 1 Lẹ́yìn náà, Ẹ̀mí gbé Jesu lọ sí aṣálẹ̀ kí Èṣù lè dán an wò. 2 Lẹ́yìn tí ó ti gbààwẹ̀ tọ̀sán-tòru fún ogoji ọjọ́, ebi…

MATIU 5

Iwaasu Jesu lórí Òkè 1 Nígbà tí Jesu rí ọ̀pọ̀ eniyan, ó gun orí òkè lọ. Ó jókòó; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ bá lọ sọ́dọ̀ rẹ̀. Àwọn tí Ayọ̀ Wà fún…

MATIU 6

Ẹ̀kọ́ nípa Ìtọrẹ Àánú 1 “Ẹ ṣọ́ra nígbà tí ẹ bá ń ṣe iṣẹ́ ẹ̀sìn yín, ẹ má máa hùwà ṣe-á-rí-mi, kí àwọn eniyan baà lè rí ohun tí ẹ̀…

MATIU 7

Ẹ̀kọ́ nípa Dídá Ẹlòmíràn Lẹ́jọ́ 1 “Ẹ má ṣe dá eniyan lẹ́jọ́, kí Ọlọrun má baà dá ẹ̀yin náà lẹ́jọ́. 2 Nítorí irú ẹjọ́ tí ẹ bá dá eniyan ni…

MATIU 8

Adẹ́tẹ̀ kan Rí Ìwòsàn 1 Nígbà tí Jesu sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè, ọ̀pọ̀ àwọn eniyan ń tẹ̀lé e. 2 Ẹnìkan tí ó ní àrùn ẹ̀tẹ̀ sì wá, ó kúnlẹ̀ níwájú…

MATIU 9

Jesu Wo Arọ kan Sàn 1 Jesu wọ inú ọkọ̀, ó rékọjá sí òdìkejì òkun, ó bá dé ìlú ara rẹ̀. 2 Àwọn kan bá gbé arọ kan wá, ó…

MATIU 10

Jesu fún Àwọn Ọmọ-ẹ̀yìn Mejila Láṣẹ 1 Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila sọ́dọ̀, ó fún wọn ní àṣẹ láti máa lé àwọn ẹ̀mí èṣù jáde, ati láti máa ṣe…

MATIU 11

1 Lẹ́yìn tí Jesu ti fi gbogbo ìlànà wọnyi lélẹ̀ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ mejila tán, ó kúrò níbẹ̀ lọ sí àwọn ìlú wọn, ó ń kọ àwọn eniyan ó…